FIRST BAPTIST CHURCH OKELERIN OGBOMOSO

FIRST BAPTIST CHURCH OKELERIN OGBOMOSO This is the official page of First Baptist Church Okelerin Ogbomosho Oyo State

25/05/2026

PRAYER BURDEN FOR THE DAY/ATENUMO ADURA FUN OJO TO 'NI
(TUESDAY MAY 26, 2026)

Ask God to help you thirst and hunger continually after Him and to remain focused on your relationship with Him (Philippians 3:12-14)./ Beere ki Olorun ran o l’owo ki o le e ma a fi igba gbogbo poungbe, ki o si ma a ni ebi si ona Re, ati lati ma a ni afojusun si ibasepo pelu Re (Filipi 3:12-14).

25/05/2026

SEEK DAILY (NBC)

Tuesday, May 26

RBT Passage: Esther 6-10

GLADNESS IN THE HOUSE OF THE LORD

Memory Verse: "I rejoiced with those who said to me, 'Let us go to the house of the LORD. Psalm 122:1, NIV

Text: Psalm 122

Psalms 122:1-8 NIV
[1] I rejoiced with those who said to me, “Let us go to the house of the Lord.”

[2] Our feet are standing in your gates, Jerusalem.

[3] Jerusalem is built like a city that is closely compacted together.

[4] That is where the tribes go up— the tribes of the Lord— to praise the name of the Lord according to the statute given to Israel.

[5] There stand the thrones for judgment, the thrones of the house of David.

[6] Pray for the peace of Jerusalem: “May those who love you be secure.

[7] May there be peace within your walls and security within your citadels.” [8] For the sake of my family and friends, I will say, “Peace be within you.”

_________________________________
Saint Augustine wrote, "In the house of God, there is a never-ending festival; the angel choir makes an eternal holiday; the presence of God's face gives joy that never fails."

Psalm 122 is one of the fifteen songs of ascent, also called the pilgrim song. These songs are usually sung by Jews when they are traveling to the city of Jerusalem. Jerusalem was the place where the temple was built, and many Jews visited the city annually for the Jewish festival. This psalm begins with gladness for an invitation to God's house but is composed as a prayer for Jerusalem. The prayer focuses on the peace and prosperity of Jerusalem. God is omnipresent, but His presence is manifested in the midst of His people. When two or more people are gathered for prayer, worship, and fellowship around God's Word, the presence of God is there. In God's presence, there is fullness of joy.

Like the psalmist, we should be glad when we go to worship God in His house. As you pray, praise, and worship God in the beauty of His holiness, your burdens will be lifted and hard-pressed issues of life will melt away. So, learn to rejoice in the presence of the Lord. Let your sorrowful heart become joyful in His presence.

_________________________________
Insight: The presence of God in His house should make you glad to meet there.

Prayer: Dear Lord, I key into the joy and gladness in Your presence always.

25/05/2026

DAILY ENCOUNTER WITH GOD (2026)

MAY 26 TUESDAY, 2026

GLADNESS IN THE HOUSE OF THE LORD

Text: Psalm 122

I rejoiced with those who said to me, "Let us go to the house of the LORD." Psalm 122:1, NIV

BH 382: I Love Thy Kingdom, Lord

RBT: Esther 6-10

A poster with two pictures has a man in rags on the right, sitting on the sidewalk with a cup in his hand and on the left is another man in rags sitting on the sidewalk with a cup in his hand, with a caption, "One failed to prepare; the other prepared to fail." The outcome was the same. Those who do not prepare to succeed are preparing to fail. In life, preparation makes the difference between success and failure.

The psalmist expressed profound joy at the invitation to the house of the Lord. He is happy to nurture relationships and celebrate love in unity of worship that fosters fellowship with God and with one another. He emphasises the importance of assembling in worship in God's presence. Worship is not merely an individual act but a collective experience that reinforces our unity as a community of believers. The house of the Lord symbolises safety, peace and shared purpose, reminding us that our faith thrives in fellowship. The house of God is a place where worship is core and joy is from God.

Like the psalmist, prioritise gathering with fellow believers by embracing the joy of worship as a shared experience rather than a solitary one. Attend church services and participate in community events that foster spiritual growth and connection. As you fellowship with others, you cultivate an atmosphere of gladness and support. Through worshipping together, you deepen your relationship with God and strengthen the bond that unites us as His people.

■ Wisdom: Unity in worship unlocks joy, harmony, and God's presence, reflecting heaven's beauty on earth.

■ Food for Thought: What role does corporate worship play in your life?

■ Follow-up Action: Be willing to play a significant role in your church's corporate worship.

■ Prayer: Father, help me to worship You all the days of my life.

Pray for these ordained ministers and members of their churches: Ajisafe E. Ajoke, Ogun; Yakubu B. Fakan, Minna; Daniel Akinloye, Suleja; Stephen A. Adediran, Igboho; Joseph A. Adedokun, Ogbomoso; Akinola Oluwadamilare M., Abeokuta; Olateju S. Olaniran, Lagos; Timothy O. Ogunleke, Ogbomoso; Babatunde E. Olaoye, Ogbomoso; M. O. Ogunwuyi, Ajagunlaase; Simeon O. Olaniyi, Ibadan; GeofferyKambai, Abuja; John A. Peter, Oyo.

Lord, destroy all the plans of the enemies over my life and family.

MAY PRAYER SHOWERS: All our daughters will not lack the right mate in the name of Jesus (Isaiah 34:16)

25/05/2026

BIBA OLORUN PADE LOJOOJUMO 2026

MAY 26 TUESDAY, 2026

INU DIDUN NINU ILE OLUWA

Bibeli Kika: Orin Dafidi 122

Inu mi dùn nigba ti won wi fun mi pe, Ẹ je ki a lọ si ile Oluwa. Orin Dafidi 122:1

YBH 136: “Gbogbo Aye Gbe Jesu Ga"

KBJL: Esteri 6-10

Iwe a-le-mogiri kan ni aworan meji ti okan je aworan okunrin kan ti o wo a*o akiṣa, o jokoo si egbe ona pelu ife kan ni owo re otun, aworan keji ję ti okunrin miiran ti oun naa wo akiṣa ti o jokoo ni egbe ona pelu ife kan ni owo re, pelu akole kan pe "Okan kuna lati murasile ; nigba ti ekeji mura lati kuna." ti ko mura sile

Atubotan re je bakan naa. Awọn lati se aseyori n murasile lati kuna. Ninu igbe-aye, imurasile lo maa n fi iyato han laarin aşeyori ati ikuna.

Onisaamu fi ayo ti o jinle han si pipe ti a pe e si ile Oluwa. Inu re dun lati mojuto ibaṣepo, o si fe lati se ajoyo ifẹ ti o wa ninu isokan ijosin eyi ti on mu idapo pelu Olorun ati awọn miiran dagba. O se atenumo iṣe-pataki pipejopo ninu ijosin niwaju Olorun. Ijosin kii kan se ohun ti enikan maa n dașe, ṣugbọn o je iriri apapo eyi ti on ro isokan wa gege bi awujo onigbagbo lagbara. Ile Oluwa n duro fun aabo, alaafia ati ibi ti a ti n se alabaapin ete, eyi ti on ran wa leti pe igbagbo wa a maa gbile ninu idapo. Ile Olorun je ibi ti ijosin ti se pataki, ti ayo si maa n ti odo Olorun wa.

Gege bii onisaamu naa, mu ipejopo pelu awon onigbagbo yooku ni okunkundun nipa titewogba ayọ ti n be ninu ijosin gege bi iriri ti a se alabaapin dipo eyi ti a n daṣe. Rii daju pe on lo si awọn eto ijosin ijọ rẹ, ki o si ko ipa ti o joju ninu awon ohun ti on lo ni awjo ti ole mu idagba*oke nipa ti emi ati a*omo wa. Bi o ti n ni idapo pelu awon miiran, se agbekale agbegbe ti o kun fun idunnu ati atileyin. Nipase jijosin papo, on mu ibasepo re pelu Olorun jinle sii, bakan naa, o n ro ibasepo ti o so wa po gege bi eniyan Re lagbara sii.

• Oro Ogbon: Isokan ninu ijosin maa n silekun ayo, irepo ati iwalaaye Olorun, o si n fi ewa orun han lori aye.

• Oro fun Ironu: Kin ni ipa ti ijosin alajosepo n ko ninu aye re?

• Ise Şişe: Şetan lati ko ipa ti o ṣe pataki ninu ijosin alajosepo ijo re.

• Adura Baba, ran mi lowo lati maa sin O ni gbogbo ojo aye mi.

Gbadura fun awon Eni-owo wonyi, idile, ati awọn ọmọ ijo Olorun: Ajisafe E. Ajoke, Ogun; Yakubu B. Fakan, Minna; Daniel Akinloye, Suleja; Stephen A. Adediran, Igboho; Joseph A. Adedokun, Ogbomoso; Akinola Oluwadamilare M., Abeokuta; Olateju S. Olaniran, Eko; Timothy O. Ogunleke, Ogbomoso; Babatunde E. Olaoye, Ogbomoso; M. O. Ogunwuyi, Ajagunlaase; Simeon O. Olaniyi, Ibadan; Geoffery Kambai, Abuja; John A. Peter, Oyo.

Oluwa, ba gbogbo ete awon ota je lori aye ati idile mi.

EBĘ ADURA FUN MAY: Gbogbo awon omobinrin wa yoo ri ọkọ gidi fẹ ni oruko Jesu (Isaiah 34:16).

24/05/2026

PRAYER BURDEN FOR THE DAY/ATENUMO ADURA FUN OJO TO 'NI
(MONDAY MAY 25, 2026)

Lord, broaden the vision of our Pastor for the end-time harvest of souls to Your Kingdom (Acts 16:9-10)./ Oluwa, mu iran Oluso-agutan wa gbooro si fun ikore okan ni igba ikehin yi si Ijoba Re (Ise Aposteli 16:9-10).

24/05/2026

*SEEK DAILY (NBC)*

*Monday, May 25, 2026*

*LET US SING TO THE LORD*

*Golden Text:* “Come, let us sing for joy to the Lord; let us shout aloud to the Rock of our salvation.”
— Psalm 95:1, NIV

*Text: Psalm 95:1-11*

[1] Come, let us sing for joy to the Lord; let us shout aloud to the Rock of our salvation.

[2] Let us come before him with thanksgiving and extol him with music and song.

[3] For the Lord is the great God, the great King above all gods.

[4] In his hand are the depths of the earth, and the mountain peaks belong to him.

[5] The sea is his, for he made it, and his hands formed the dry land.

[6] Come, let us bow down in worship, let us kneel before the Lord our Maker;

[7] for he is our God and we are the people of his pasture, the flock under his care. Today, if only you would hear his voice,

[8] “Do not harden your hearts as you did at Meribah, as you did that day at Massah in the wilderness,

[9] where your ancestors tested me; they tried me, though they had seen what I did.

[10] For forty years I was angry with that generation; I said, ‘They are a people whose hearts go astray, and they have not known my ways.’

[11] So I declared on oath in my anger, ‘They shall never enter my rest.’ ”

________

In the midst of a bustling street with traffic noise, a man heard a sweet voice singing melodiously.

He could not ignore the sound. On finding the singer, he was surprised to discover he had no legs.

The man told the singer, “Hearing your sweet voice even in this condition has reminded me that I have much to be grateful for.”

The man replied, “When I stopped thinking about what I had lost and began concentrating on all I had left, I found much rea*on to rejoice.”

The psalmist enjoins us to sing to the Lord. He highlights how and why we should sing to the Lord.

We are to sing joyfully with thanksgiving, music, shouting, and adoration.

We are to sing to the Lord because of His greatness, creative ingenuity, kingship and fatherly love.

God deserves our praise always. We must engage in singing to our God in all circumstances.

We are called to sing to the Lord in clear understanding of His might and majesty, and not from emotions.

As you sing, let your focus be on the Lord who is the object and subject of your songs.

Freely express your heartfelt gratitude to Him after deep reflection on His greatness, goodness, and care. Sing aloud to proclaim the name of the Lord.

*Insight:* Singing is one of the simplest forms of worship.

*Prayer:* Father, fill my heart with songs that honour and glorify You.

*RBT Passage: Esther 1-5*

24/05/2026

*DAILY ENCOUNTER WITH GOD (NBC)*

*WEEK 22: May 31, 2026*

*GOLDEN TEXT:* "And let us consider how we may spur one another on towards love and good deeds." Hebrews 10:24.

*PROVOKE ONE ANOTHER.*

*Text: Hebrews 10:22-25.*

*DAILY ENCOUNTER WITH GOD (NBC)*

*MONDAY, MAY 25 , 2026*

*LET US SING TO THE LORD*

*BH: 20: O Worship the King*

1. O worship the King, all glorious above,
And gratefully sing His wonderful love;
Our shield and defender, the
Ancient of days
Pavilioned in splendor and girded with praise.

2. O tell of His might, O sing of His grace,
Whose robe is the light, whose canopy space!
His chariots of wrath the deep
thunder clouds form,
And dark is His path on the wings of the storm.

3. Thy bountiful care what tongue can recite?
It breathes in the air, it shines in the light,
It streams; from the hills, it descends to the plain,
And sweetly distils in the dew and the rain.

4. Frail children of dust, and feeble as frail,
In Thee do we trust, nor find Thee to fail
Thy mercies how tender, how firm to the end,
Our maker, Defender, Redeemer, and Friend. Amen.

*Golden Text:* Come, let us sing for joy to the LORD; let us shout aloud to the Rock of our salvation. Psalm 95:1, NIV

*Text: Psalm 95:1-11*

[1] Come, let us sing for joy to the Lord; let us shout aloud to the Rock of our salvation.

[2] Let us come before him with thanksgiving and extol him with music and song.

[3] For the Lord is the great God, the great King above all gods.

[4] In his hand are the depths of the earth, and the mountain peaks belong to him.

[5] The sea is his, for he made it, and his hands formed the dry land.

[6] Come, let us bow down in worship, let us kneel before the Lord our Maker;

[7] for he is our God and we are the people of his pasture, the flock under his care. Today, if only you would hear his voice,

[8] “Do not harden your hearts as you did at Meribah, as you did that day at Massah in the wilderness,

[9] where your ancestors tested me; they tried me, though they had seen what I did.

[10] For forty years I was angry with that generation; I said, ‘They are a people whose hearts go astray, and they have not known my ways.’

[11] So I declared on oath in my anger, ‘They shall never enter my rest.’ ”
________

D. A. Carson said, "Worship is the proper response of all moral, sentient beings to God, ascribing all honour and worth to their Creator-God precisely because he is worthy, delightfully so."

Worship is not just a ritual, but it is a reflection of our relationship with God.

King David in today's text highlighted the importance of genuine worship.

The psalmist invites us to join in a joyful expression of praise.

This call is divided into two parts; the first is a call to sing, shout, and bow before the Lord, acknowledging His majesty, creation, and redemption.

The second part serves as a warning, cautioning against the hardening of hearts and rebellion, referencing Israel's wilderness experience.

Worship sets us apart from the context of our immediate environment; it places us in another realm in alignment with God if properly done.

Therefore, you should engage wholeheartedly in worship, expressing gratitude and adoration.

By joining others in united worship, you strengthen fellowship and unity, declaring God's worthiness to the world.

Apply this truth by cultivating a lifestyle of genuine worship, honouring God in every aspect of your life, and fostering meaningful relationships with fellow believers through shared worship experiences.

*Wisdom:* God delights in the worship of His children.

*Food for Thought:* Are you a genuine worshiper of God?

*Follow-up Action:* Worship God with some new songs today.

*Prayer:* Lord God, I worship You for who You are to me and my family. May Your name forever be praised.

*Prayer:* Lord, may I not deny myself from enjoying the privileges I have in You.

*Pray for these ordained ministers and members of their churches:*
Ruth Odejayi, Ibadan; Sunday Auta, Fadama; Deborah N. Adedoja, Kaduna; Joel O. Odesoji, Ogijo; Dada Ajibola, Lagos; Adeoye Isaac, Ogun; Daniel M. Kashama, Uragi; Adisa L. Adeoyin, Ogboro; Olatubosun A. Gbenga, Saki; Adedara V. Adeoye, Abidjan; Michael A. Oguntoye, Osogbo; Olayinka S. Olatunji, Lagos; Oyunniyi A. Philip, Ogun; P. I. Bangbose, Ogun; Daniel V. Francis, Ang. Habu; Adesola P. Adeola, Rivers; Prince U. F. Ihedike, Rivers; Peter O. Siyanbola, Ibadan; Kehinde Rotimi, Kogi; S. A. Asamu, Ogbomoso; Oyekunle Ebenezer, Ogbomoso; Wole Ajao, Ogbomoso; Isaac Adebayo, Ogbomoso; Oni O. Joshua, Ogbomoso; Ajala John A., Ogbomoso; Iyanda S. Imole, Ogbomoso; Ebireri G. Obireri, Eku; Oleabhie Paul A., Edo; Felicia E. Odjesawha, Ughelli; Ayankanmi J. Temitope, Ilora; A. E. Oladele, Oyo; Oyelaran O. K. Michael, Ede; Oparinde Matthew O., Ede; Ogunlola S. Olatunji, Yobe; Edward K. Afolabi, Ibadan; Simon D. Kdrau, Malaki; Victor Sako, Huri; Caleb B. Sodangi, Bege; Rufai Ishaya, Malumfashi; Jeasulowo O. Emmanuel, Eleyin.

*RBT: Esther 1-5*

24/05/2026

*BIBA OLORUN PADE LOJOOJUMO (NBC YORUBA)*

*OSẸ KEJI-LE-LOGUN:*

*Sunday, May 31, 2026.*

*RIRU ARA-ẸNI SOKE.*

*Bibeli Kika: Heberu 10:22-25.*

*ẸSẸ LATI RANTI:* "Ẹ jẹ ki a yẹ ara wa wo lati rú ara wa si ifẹ ati si iṣẹ rere:" Heberu 10:24

*BIBA OLORUN PADE LOJOOJUMO (NBC YORUBA)*

*MONDAY, MAY 25, 2026*

*Ẹ JẸ KI A KỌRIN SI OLUWA*

*YBH 8: Ẹ Wọle F'Ọba*

1. Ewole f’ Oba, ologo julo,
E korin ipa ati ife Re;
Alabo wa ni, at’ Eni Igbani,
O ngbe ‘nu ogo, eleru ni iyin.

2. E so t’ ipa Re, e so t’ ore Re:
‘Mole l’ a*o Re gobi Re orun,
B’ ara ti nsan ni ‘keke, ibinu Re;
Ipa ona Re ni a ko si le mo.

3. Aiye yi pelu ekun re gbogbo,
Olorun, agbara Re l’ o da won:
O fi idi re mu ‘le, ko si le yi,
O si f’ okun se oja igbaiya re.

4. Itoju Re wa lara gbogbo won,
Ninu afefe, ninu imole;
Itoju Re wa ninu ‘ odo ti o nsan,
O si wa ninu iri ati ojo.

5. Awa erupe, aw’ alailera,
‘Wo l’ a gbekele, O ki o da ni;
Anu Re ronu, o si le de opin
Eleda, Alabo, Olugbala wa.

6. ‘Wo alagbara, onife julo,
B’ awon angeli ti yin O loke,
Be l’ awa eda Re niwon t’ a le se
A o ma juba Re, a o ma yin O.

*Ese Lati Ranti:* Ẹ wá, ẹ jẹ ki a kọrin si Oluwa: ẹ jẹ ki a hó iho ayọ si apata igbala wa. Orin Dafidi 95:1

*Bibeli Kika: Orin Dafidi 95:1-11*

[1] ẸWÁ, ẹ jẹ ki a kọrin si Oluwa: ẹ jẹ ki a hó iho ayọ̀ si apata igbala wa.

[2] Ẹ jẹ ki a fi ọpẹ wá si iwaju rẹ̀, ki a si fi orin mimọ́ hó iho ayọ̀ si ọdọ rẹ̀.

[3] Nitori Oluwa, Ọlọrun ti o tobi ni, ati Ọba ti o tobi jù gbogbo oriṣa lọ,

[4] Ni ikawọ ẹniti ibi ọgbun ilẹ wà: giga awọn òke nla ni tirẹ̀ pẹlu.

[5] Tirẹ̀ li okun, on li o si dá a: ọwọ rẹ̀ li o si dá iyangbẹ ilẹ.

[6] Ẹ wá, ẹ jẹ ki a wolẹ, ki a tẹriba: ẹ jẹ ki a kunlẹ niwaju Oluwa, Ẹlẹda wa.

[7] Nitori on li Ọlọrun wa; awa si li enia papa rẹ̀, ati agutan ọwọ rẹ̀. Loni bi ẹnyin o ba gbọ́ ohùn rẹ̀,

[8] Ẹ má sé aiya nyin le, bi ti Meriba ati bi ọjọ na ni Massa, li aginju.

[9] Nigbati awọn baba nyin dan mi wò, ti nwọn wadi mi, ti nwọn si ri iṣẹ mi.

[10] Ogoji-ọdun tọ̀tọ ni inu mi fi bajẹ si iran na, mo ni, Enia ti o ṣina li aiya ni nwọn, nwọn kò si mọ̀ ọ̀na mi:

[11] Awọn ẹniti mo si bura fun ni ibinu mi pe, nwọn ki yio wọ ibi isimi mi.

________

D.A. Carson wi pe "Ijosin jẹ ọna ti o tọ lati kọ iha ti o tọ si gbogbo didara Ọlọrun, ki a fi gbogbo ọla ti o tọ ati eyi ti o yẹ fun Ẹlẹdaa wọn—Ọlọrun, nitori pe Oun ni o tọ si."

Ijosin kii kan ṣe eto to ti di baraku, ṣugbọn o jẹ iwoye ti a ni nipa ibasẹpọ wa pẹlu Ọlọrun.

Ninu ẹṣẹ Bibeli ti oni, Dafidi Ọba mọnu ba iṣẹ-pataki ijosin tootọ. Onisaamu yii n pe wa lati darapọ ninu fifi ayọ yin Ọlọrun.

Ipe yii pin si oriṣii ọna: akọkọ jẹ ipe lati kọrin, ho ati lati wọle niwaju Oluwa, ki a mọ riri ọlanla, iṣẹda ati irapada Rẹ.

Ọna keji jẹ ikilọ lati mase ṣe aya le, ki a ma si ṣe ọtẹ, gẹgẹ bi o ṣe tọka si iriri awọn ọmọ Isrẹli ni aginjù.

Ijosin maa n gbe wa kuro ni agbegbe ti a wa lọ si ibomiran lati ni imọlara ifarakinra pẹlu Ọlọrun bi a ba ṣe e bi o ti yẹ.

Nitori naa, o gbọdọ fi gbogbo ọkan rẹ jọsin, ki o fi ẹmi imoore ati iyin jọba han.

Nígba ti o ba n darapọ mọ awọn miiran lati jọsin, o n ro idapọ ati iṣọkan lagbara, o si n kede yiye Ọlọrun fun araye.

Ṣe amulo otitọ yii nipa siso ijosin tootọ di ọna igbe-aye rẹ, maa bu ọla fun Ọlọrun ni gbogbo agbọn aye rẹ, ki o si maa mu ibasẹpọ ti o nitumọ dagba pẹlu awọn onigbagbọ akẹgbẹ rẹ nipasẹ ṣiṣe alabaapin awọn iriri ijosin papọ.

*Ọrọ Ọgbọn:* Ọlọrun ni inu-didun ninu ijosin awọn ọmọ Rẹ.

*Ọrọ fun Ironu:* Njẹ o jẹ olujọsin tootọ si Ọlọrun?

*Iṣẹ Ṣiṣe:* Fi awọn orin tuntun jọsin si Ọlọrun loni.

*Adura:* Oluwa Ọlọrun, mo yin Ọ fun ẹni ti O jẹ si mi ati ibikitá Rẹ lori emi ati idile mi. Jẹ ki orukọ Rẹ di ayinlogo t**i lae.

*Adura:* Oluwa, ma jẹ ki n dun ara mi ni awọn anfaani ti mo ni ninu Rẹ.

*Gbadura fun awọn Ẹni-ọwọ wọnni, idile, ati awọn ọmọ ijọ Ọlọrun:*
Ruth Odejayi, Ibadan; Sunday Auta, Fadama; Deborah N. Adedọja, Kaduna; Joel O. Odesọji, Ogijo; Dada Ajibọla, Eko; Adeoye Isaac, Ogun; Daniel M. Kashama, Uragi; Adisa L. Adedoyin, Ogbooro; Olatubọsun A. Gbenga, Ṣaki; Adedara V. Adeoye, Abidjan; Michael A. Oguntoye, Oṣogbo; Ọlayinka S. Ọlatunji, Eko; Oyunniyi A. Philip, Ogun; P. I. Bangbose, Ogun; Daniel V. Francis, Ang. Habu; Adeṣọla P. Adeọla, Rivers; Prince U. F. Ihedike, Rivers; Peter O. Siyanbọla, Ibadan; Kehinde Rotimi, Kogi; S. A. Asamu, Ogbomọṣọ; Oyekunle Ebenezer, Ogbomọṣọ; Wọle Ajao, Ogbomọṣọ; Isaac A., Ogbomọṣọ; Iyanda S. Imọlẹ, Ogbomọṣọ; Ajala John Eku; Oleahbie Paul A., Edo; Felicia E. Odjesawha, Ughelli; Ayankanmi J. Temitọpẹ, Ilọra; A. E. Ọladẹlẹ, Ọyọ; Oyelaran O. K. Michael, Ẹdẹ; Ọparinde Matthew O., Ẹdẹ; Ogunlola S. Olatunji, Yobe; Edward K. Afọlabi, Ibadan; Simon D. Kdrau, Malaki; Victor Sako, Huri; Caleb B. Sodangi, Bẹgẹ; Rufai Ishaya, Malumfashi; Jesulọwọ O. Emmanuel, Ẹlẹyin.

*KBJL: Esteri 1-5*

Today’s children’s service was a beautiful reminder that God cares deeply about every little heart. 🤍 Picture Excerpt 📸 ...
24/05/2026

Today’s children’s service was a beautiful reminder that God cares deeply about every little heart. 🤍

Picture Excerpt 📸

24/05/2026

2026 CHILDREN'S DAY SERVICE |THE HOLY SPIRIT EQUIPS CHRISTAINS FOR LIFESTYLE AND SERVICE| 24.05.2026

Address

FIRST BAPTIST CHURCH OKELERIN
Ogbomosho
234

Alerts

Be the first to know and let us send you an email when FIRST BAPTIST CHURCH OKELERIN OGBOMOSO posts news and promotions. Your email address will not be used for any other purpose, and you can unsubscribe at any time.

Share